Nọ́ḿbà 3:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kí o sì yan Árónì àti àwọn ọmọ rẹ̀ láti máa ṣiṣẹ́ àlùfáà; ẹnikẹ́ni tó bá súnmọ́ ibi mímọ́ pípa ni kí ẹ pa á.”

Nọ́ḿbà 3

Nọ́ḿbà 3:9-14