Nọ́ḿbà 26:22-26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

22. Wọ̀nyí ni ìdílé Júdà; gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá méjìdínlógójì ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta. (76,500).

23. Àwọn ọmọ Isákárì gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:ti Tólà, ìdílé Tólà;ti Púfà, ìdílé Púfà;

24. ti Jáṣúbù, ìdílé Jáṣúbù;ti Ṣímírónì, ìdílé Ṣímírónì.

25. Wọ̀nyí ni ìdílé Isákárì gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàáméjìlélọ́gbọ̀n ó léọ̀ọ́dúnrún (64,300).

26. Àwọn ọmọ Ṣebúlúnì gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:ti Sẹ́rẹ́dì, ìdílé Ṣẹ́rẹ́dì;ti Élónì, ìdílé Élónì;ti Jálélì, ìdílé Jálélì.

Nọ́ḿbà 26