Nọ́ḿbà 22:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Olórí àwọn Móábù àti Mídíánì sì lọ pẹ̀lú owó àyẹ̀wò lọ́nà wọn, Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Bálámù, wọ́n sọ nǹkan tí Bálákì sọ fún wọn.

Nọ́ḿbà 22

Nọ́ḿbà 22:1-16