Nọ́ḿbà 21:24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àmọ́ Ísírẹ́lì ṣẹ́gun, wọn fi ojú idà pa wọ́n, wọ́n sì gba ilẹ̀ láti ọwọ́ Ánónì lọ dé Jábókù, títí tí ó fi dé ilẹ̀ àwọn ará Ámónì, nítorí pé ààlà wọn jẹ́ olódi.

Nọ́ḿbà 21

Nọ́ḿbà 21:15-34