Nọ́ḿbà 16:39 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Élíásárì tí í ṣe àlùfáà sì kó gbogbo àwo tùràrí tí àwọn tí ó jóná mú wa, ó gún wọn pọ̀, ó fi ṣe ìbòrí fún pẹpẹ,

Nọ́ḿbà 16

Nọ́ḿbà 16:35-42