Nọ́ḿbà 15:39 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wò láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbérè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.

Nọ́ḿbà 15

Nọ́ḿbà 15:32-41