Nehemáyà 12:1-8 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Léfì tí ó bá Ṣérúbábélì ọmọ Ṣéálítíélì àti Jéṣúà padà:Ṣeraiáyà, Jeremáyà, Éṣírà,

2. Ámáríyà, Málúkì, Hátúsì,

3. Ṣekánáyà, Réhúmù, Mérémótì,

4. Ídò, Gínétónì, Ábíjà,

5. Míjámínì, Móádáyà, Bílígà,

6. Ṣémááyà, Jóíáríbù, Jédááyà,

7. Ṣálù, Ámókì, Hílíkíyà, àti Jédáyà.Wọ̀nyí ni olóórí àwọn àlùfáà àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn ní ìgbà ayé e Jéṣúà.

8. Àwọn ọmọ Léfì ni Jéṣúà, Bínúì, Kádímálì, Ṣérébíà, Júdà àti Mátaníyà ẹ̀ni tí òun pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀, ni àkóso orin ìdúpẹ́.

Nehemáyà 12