Nehemáyà 11:16 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣábétaì àti Jóṣábádì, olórí méjì nínú àwọn ọmọ Léfì, àwọn tí ó jẹ́ alábojútó iṣẹ́ tí ó wà ní ẹ̀yìn àgbàlá ilé Ọlọ́run;

Nehemáyà 11

Nehemáyà 11:7-23