Jóṣúà 4:3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

kí o sì pàṣẹ fún wọn pé Ẹ gbé òkúta méjìlá (12) láti àárin odò Jọ́dánì ní ibi tí àwọn àlùfáà dúró sí, kí ẹ sì rù wọn kọjá, kí ẹ sì gbé wọn sí ibi tí ẹ̀yin yóò sùn ní alẹ́ yìí.”

Jóṣúà 4

Jóṣúà 4:1-11