1. Ígbà náà ni Bílídádì, ará Ṣúà, sì dáhùn wí pé:
2. “Ìwọ yóò ti máa sọ nǹkán wọ̀nyí pẹ́ tó?Tí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ yóò sì máa bí ẹ̀fúùfú ńlá?
3. Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí,tàbí Olódùmárè a máa fi òtítọ́ sẹ̀ bí?
4. Nígbà tí àwọn ọmọ rẹ̀ sẹ̀ sí i,ó sì gbá wọn kúrò nítorí àṣẹ wọn.