1. Olúwa dá Jóòbù lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wi pé:
2. “ẹni tí ń wá ẹ̀sùn yóò bá Olódùmarè wíjọ́ bí?Ẹni tí ń bá Ọlọ́run jiyàn jẹ́ kí ó dáhùn!”
3. Nígbà náà ni Jóòbù dá Olúwalóhùn wá ó sì wí pé,
4. “Kíyèsí i, èmi kò jámọ́ ohun kankan;ohun kí ni èmi ó dà? Èmi ó fi ọwọ́ le ẹnu mi.