22. Nitorí kí ni ẹ̀yin ṣe lépa mi bíỌlọ́run, tí ẹran ara mi kò tẹ́ yín lọ́rùn?
23. “Áà! Ìbáṣe pé a le kọ̀wé ọ̀rọ̀ minísinsìn yìí, ìbáṣepé a le dà á sínú ìwé!
24. Kí a fi kálàmú irin àti ti òjé kọwọ́n sínú àpáta fún láéláé.
25. Nítorí èmi mọ̀ pé olùdáùndè miń bẹ láàyè àti pe òun ni yóò dìdedúró lórí ilẹ̀ ní ìkẹyìn;
26. Àti lẹ́yìn ìgbà tí a pa àwọ̀ arami run, síbẹ̀ láìsí ẹran ara mi ni èmi ó rí Ọlọ́run,
27. Ẹni tí èmi ó rí fún ara mi, tí ojúmi ó sì wo, kì sì íṣe tiẹlòmìíràn; ọkàn mi sì dákú ní inú mi.
28. “Bí ẹ̀yin bá wí pé, ‘àwa ó ti lépa rẹ̀ tó!Àti pé, gbogbo ọ̀rọ̀ náà ni a ṣáà rí ní ọwọ́ rẹ̀,’