Jeremáyà 51:52-54 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

52. “Nítorí náà, wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,“tí èmi yóò se ìbẹ̀wò lórí àwọn ère fífin rẹ̀:àti àwọn tí ó gbọgbẹ́ yóò sì máa gbin já gbogbo ilẹ̀ rẹ̀

53. Bí Bábílónì tilẹ̀ gòkè lọ sí ọ̀run,bí ó sì ṣe ìlú olodi ní òkè agbára rẹ,síbẹ̀ àwọn afiniṣèjẹ yóò ti ọ̀dọ̀ mi tọ̀ ọ́ wá,”ní Olúwa wí.

54. “Ìró igbe láti Bábílónì,àti ìparun láti ilẹ̀ àwọn ará Kálídéà!

Jeremáyà 51