Jeremáyà 10:1-3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ fún yín ẹ̀yin ilé Ísírẹ́lì.

2. Èyí ni ohun tí Olúwa wí:“Má se tọ ọ̀nà àwọn orílẹ̀ èdètàbí kí ẹ jẹ́ kí àmù òfuurufú dààmúyín, nítorí pé wọ́n ń dààmú orílẹ̀ èdè.

3. Nítorí pé asán ni asà àwọn ènìyàn,wọ́n gé igi láti inú igbó, oníṣẹ́-ọnàsì gbẹ́ ẹ pẹ̀lú àáké rẹ̀.

Jeremáyà 10