Jẹ́nẹ́sísì 24:36 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣárà aya olúwa mi sì ti bí ọmọkùnrin kan fún un, ní ìgbà ogbó rẹ̀, olúwa mi sì ti fún ọmọ náà ní ohun gbogbo tí ó ní.

Jẹ́nẹ́sísì 24

Jẹ́nẹ́sísì 24:31-42