Ẹ́sírà 10:23-28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

23. Lára àwọn ọmọ Léfì:Jósábádì, Ṣíhíméì, Kéláéáyà (èyí tí í se Kélítà), Pétíáíyà, Júdà àti Élíásérì.

24. Nínú àwọn akọrin:Élíásíbù.Nínú àwọn asọ́nà:Sálúmù, Télémù àti Úrì.

25. Àti lára àwọn ọmọ Ísírẹ́lì tókù:Nínú ìran Párósì:Rámíáyà, Ísíáyà, Málíkíjà, Míjámínì, Éléásánì, Málíkíjà àti Bénáíyà.

26. Nínú ìran Élámù:Mátaníáyà, Ṣékáríáyà, Jéhíélì, Ábídì, Jérémótì àti Élíjà.

27. Nínú àwọn ìran Ṣátítù:Élíóénáì, Élísíbù, Mátaníáyà, Jérémótì, Ṣábádì àti Ásísà.

28. Nínú àwọn ìran Bébáì:Jéhóánánì, Hánánáyà, Ṣábábáì àti Átaláì.

Ẹ́sírà 10