2. Rúbẹ́nì, Símónì, Léfì àti Júdà,
3. Ísákárì, Ṣébúlúnì àti Bẹ́ńjámínì,
4. Dánì àti Náfítalì, Gádì àti Ásérì.
5. Àwọn ìran Jákọ́bù sì jẹ́ àádọ́rin ní àpapọ̀; Jóṣẹ́fù sì ti wà ní Éjíbítì.
6. Wáyìí o, Jóṣẹ́fù àti gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìran náà kú,