Deutarónómì 11:31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ẹ ti ṣetan láti la Jọ́dánì kọjá láti lè gba ilẹ̀ náà tí Olúwa Ọlọ́run yín ń fún un yín. Nígbà tí ẹ bá gbà á, tí ẹ bá sì ń gbé ibẹ̀,

Deutarónómì 11

Deutarónómì 11:24-32