Dáníẹ́lì 5:25-28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

25. “Èyí ni àkọlé náà tí a kọ:MENE, MENE, TÉKÉLÌ, PÉRÉSÍNÌ

26. “Èyí ni nǹkan tí ọ̀rọ̀ náà túmọ̀ sí: Mene: Ọlọ́run ti sírò ọjọ́ ìjọba rẹ. Ó sì ti mú u wá sí òpin.

27. Tékélì: A ti gbé ọ lórí òṣùwọ̀n, ìwọ kò sì tó ìwọ̀n.

28. Pérésínì: A ti pín ìjọba rẹ a sì ti fi fún àwọn Médíà àti àwọn Páṣíà.”

Dáníẹ́lì 5