Àwọn Hébérù 8:1-3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Nísinsin yìí, kókó ohun tí à ń sọ nìyí: Àwá ní irú olórí àlùfáà bẹ́ẹ̀, tí ó jokòó lọ́wọ́ ọ̀tún ìtẹ́ ọla ńlá nínú àwọn ọ̀run:

2. Ìránṣẹ́ ibi mímọ́, àti ti àgọ́ tóòtọ́, tí Olúwa pa, kì í ṣe ènìyàn.

3. Nítorí a fi olórí àlùfáà kọ̀ọ̀kan jẹ láti máa mú ẹ̀bùn wá láti máa rúbọ: Nítorí náà ó ṣe pàtàkì fún eléyìí náà láti ní nǹkan tí ó máa fi sílẹ̀.

Àwọn Hébérù 8