Àwọn Hébérù 5:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nípa èyí àwá ní ohun púpọ̀ láti sọ, tí ó sì ṣòro láti túmọ̀, nítorí pé ẹ yigbì ní gbígbọ́.

Àwọn Hébérù 5

Àwọn Hébérù 5:5-13