Àìsáyà 57:19-21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

19. ní dídá ìyìn sí ètè àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ní Ísírẹ́lì.Àlàáfíà, àlàáfíà fún àwọn tí ó wà lókèèrè àti nítòsí,”ni Olúwa wí, “Àti pé Èmi yóò wo wọ́n sàn.”

20. Ṣùgbọ́n àwọn ìkà dàbí i ríru òkuntí kò le è sinmi,tí ìgbì rẹ̀ ń rú pẹ̀tẹ̀pẹ́tẹ̀ àti ẹrọ̀fọ̀ sókè.

21. “Kò sí àlàáfíà,” ni Ọlọ́run mi wí, “fún àwọn ìkà.”

Àìsáyà 57