Àìsáyà 52:15 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣe bomirin àwọn orílẹ̀ èdè ká,àwọn ọba yóò sì pa ẹnu wọn mọ́ nítoríi rẹ̀.Nítorí ohun tí a kò sọ fún wọn, wọn yóò rí i,àti ohun tí wọn kò tí ì gbọ́, ni yóò sì yé wọn.

Àìsáyà 52

Àìsáyà 52:10-15