1 Ọba 8:56 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Ìbùkún ni fún Olúwa tí ó ti fi ìsinmi fún Ísírẹ́lì, ènìyàn rẹ̀ bí ó ti ṣèlérí. Kò sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ kan tí ó kùnà nínú gbogbo ìlérí rere tí ó ti ṣe láti ọwọ́ Mósè ìránṣẹ́ rẹ̀ wá.

1 Ọba 8

1 Ọba 8:50-66