1 Ọba 7:8 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ààfin rẹ̀ níbi tí yóò sì gbé wà ní àgbàlá lẹ́yìn ààfin, irú kan náà ni wọ́n. Sólómónì sì kọ́ ààfin tí ó rí bí gbàngàn yìí fún ọmọbìnrin Fáráò tí ó ní ní aya.

1 Ọba 7

1 Ọba 7:2-9