1 Ọba 22:35 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ogun náà sì le ní ọjọ́ náà, a sì dá ọba dúró nínú kẹ̀kẹ́ kọjú sí àwọn ará Árámù. Ẹ̀jẹ̀ sì sàn jáde láti inú ọgbẹ́ rẹ̀ sí àárin kẹ̀kẹ́ náà, ó sì kú ní àṣálẹ́.

1 Ọba 22

1 Ọba 22:30-45