1 Ọba 16:19 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó ti ṣẹ̀, ní ṣíṣe búburú níwájú Olúwa àti ní rírìn ní ọ̀nà Jéróbóámù àti nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó ti ṣe àti tí ó ti mú Ísírẹ́lì ṣẹ̀.

1 Ọba 16

1 Ọba 16:13-29