1 Kọ́ríńtì 5:1-2 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ìròyìn rẹ ń tàn kalẹ̀ pé ìwà, àgbérè wa láàrin yín, irú àgbérè tí a kò tilẹ̀ gbúròó rẹ̀ láàrin àwọn aláìkọlà pé, ẹnìkan nínú yín ń fẹ́ ìyàwó baba rẹ̀.

2. Ẹ̀yin ń se ìgberaga, kí ni ṣe tí ojú kò tì yín, kí ẹ sì kún fún ìbànújẹ́, kí ẹ sì rí i pé ẹ yọ ọkùnrin náà tí ó hu ìwà yìí kúrò láàrin àwọn ọmọ ìjọ yín?

1 Kọ́ríńtì 5