1 Kíróníkà 6:36-47 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

36. Ọmọ Élíkánà, ọmọ Jóẹ́lì,ọmọ Ásárááhì, ọmọ Ṣéfáníáhì

37. Ọmọ Táhátì, ọmọ Áṣírì,ọmọ Ébíásáfì ọmọ Kóráhì,

38. ọmọ Íṣíhárì, ọmọ Kóhátìọmọ Léfì, ọmọ Ísírẹ́lì;

39. Hémánì sì darapọ̀ mọ́ Ásátì, ẹni tí Ó sìn ní ọwọ́ ọ̀tún Rẹ̀:Ásátì ọmọ bérékíáhì, ọmọ Ṣíméà,

40. Ọmọ Míkáélì, ọmọ Bááséíáhì,ọmọ Málíkíjáhì

41. Ọmọ Étínì,ọmọ Ṣéráhì, ọmọ Ádáyà,

42. Ọmọ Étanì, ọmọ Ṣímáhì,ọmọ Ṣíméhì,

43. Ọmọ Jáhátì,ọmọ Gérísíónì, ọmọ Léfì;

44. láti ìbákẹ́gbẹ́ wọn, àwọn ará Mérárì wà ní ọwọ́ òsì Rẹ̀:Étanì ọmọ Kísì, ọmọ Ábídì,ọmọ Málúkì,

45. Ọmọ Háṣábíáhìọmọ Ámásáyà, ọmọ Hítíkíáhì,

46. Ọmọ Ámíṣì ọmọ Bánì,ọmọ Ṣémérì,

47. Ọmọ Máhílì,ọmọ Múṣì, ọmọ Mérárì,ọmọ Léfì.

1 Kíróníkà 6