13. Ṣálúmù baba Hílíkíyà,Hílíkíyà baba Áṣáríyà,
14. Áṣáríyà baba Ṣéráíà,pẹ̀lú Ṣéráíà baba Jéhósádákì
15. A kó Jéhósádákì lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Júdà àti Jérúsálẹ́mù kúrò ní ìlú nípaṣẹ̀ Nebukadinésárì.
16. Àwọn ọmọ Léfì:Gérísónì, kóhátì àti Mérárì.
17. Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Géríṣónì:Líbínì àti Ṣíméhì.