1 Kíróníkà 24:21-28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

21. Àti gẹ́gẹ́ bí Réhábíà, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Réhábíà:Íṣíà sì ni alákọ́kọ́.

22. Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Iṣárì: Ṣélómótì;láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Ṣélomótì: Jáhátì.

23. Àwọn ọmọ Hebúrónì: Jéríyà alákọ́kọ́, Ámáríyà elẹ́kẹjì, Jáhásélì ẹlẹ́kẹta àti Jékáméámù ẹlẹ́kẹrin.

24. Àwọn ọmọ Húsíélì: Mikà;nínú àwọn ọmọ Míkà: Ṣámírù.

25. Àwọn arákùnrin Míkà: Íṣíà;nínú àwọn ọmọ Íṣíà: Ṣekaríyà.

26. Àwọn ọmọ Mérarì: Málì àti Múṣì.Àwọn ọmọ Jásíà: Bẹ́nò.

27. Àwọn ọmọ Mérárì:Lati Jasíà: Bẹ́nò, Ṣóhámù, Ṣákúrì àti Íbírì.

28. Láti Málì: Élíásérì, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.

1 Kíróníkà 24