1 Kíróníkà 1:13-31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

13. Kénánì ni babaṢídónì àkọ́bí Rẹ̀, àti ti àwọn ará Hítì,

14. Àwọn ará Jébúsì, àwọn ará Ámórì, àwọn ará Gírígásì

15. Àwọn Hífì, àwọn ará Áríkì, àwọn ará Hamati-Ṣínì,

16. Àwọn ará Árífádù, àwọn ará, Ṣémárì, àwọn ará Hámátì.

17. Àwọn ọmọ Ṣémù:Élámù. Ásúrì, Árífákásádì, Lúdì àti Árámù.Àwọn ará Árámù:Usì Húlì, Gétérì, àti Méṣékì.

18. Árífákásádì sì jẹ́ Baba Ṣélà,àti Ṣélà sì jẹ́ Baba Ébérì.

19. A bí àwọn ọmọ méjì fún Ébérì:Orúkọ ọ̀kan ni Pélégì, nítorí ní àkókò tirẹ̀ a pín ayé; orúkọ ẹ̀gbọ́n Rẹ̀ ọkùnrin a sì máa jẹ́ Jókítanì.

20. Jókítanì sì jẹ́ Baba fúnHímódádì, Ṣéléfì, Hásárímáfétì, Jérà.

21. Hádórámì, Úsálì, àti Díkílà

22. Ébálì, Ábímáélì, Ṣébà.

23. Ófírì, Háfílà, àti Jóbábù. Gbogbo àwọn wọ̀nyí sì jẹ́ àwọn ọmọ Jókítanì.

24. Ṣémù, Árífákásádì, Sẹ́bà,

25. Ébérì, Pélégì. Réù,

26. Ṣérúgì, Náhórì, Térà:

27. Àti Ábúrámù (tí ń ṣe Ábúráhámù).

28. Àwọn ọmọ Ábúráhámù:Ísáákì àti Íṣímáẹ́lì.

29. Èyí ni àwọn ọmọ náà:Nébáíótì àkọ́bí Íṣímáẹ́lì: Kédárì, Ádíbélì, Míbísámù,

30. Míṣímà, Dúmà, Másà, Hádádì, Témà,

31. Jétúrì, Náfísì, àti Kédámù. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Íṣímáẹ́lì

1 Kíróníkà 1